Leviticus 19:36
36
Ẹ jẹ́ olódodo pẹ̀lú àwọn òṣùwọ̀n yín òṣùwọ̀n ìtẹ̀wọ̀n, òṣùwọ̀n wíwúwo, òṣùwọ̀n ìyẹ̀fun àti òṣùwọ̀n nǹkan olómi yín ní láti jẹ́ èyí tí kò ní èrú nínú. Èmi ni
Olúwa
Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti.
Copyright information for
YorBMYO